Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Àwọn Ohun Tó Jáde Láìpẹ́ Yìí

 

Ohun Méjìlá Tó Ń Mú Kí Ìdílé Láyọ̀

Tó o bá ń tẹ̀ lé àwọn ìlànà yìí, ìdílé rẹ á láyọ̀.

Awọ Ẹja Àbùùbùtán​—Ta Ló Ṣiṣẹ́ Àrà Yìí?

Báwo ni awọ ẹja àbùùbùtán ṣe máa ń dáàbò bò ó lọ́wọ́ kòkòrò àrùn?

Bó O Ṣe Lè Ní Ìtẹ́lọ́rùn àti Ìfọ̀kànbalẹ̀

Wàá rí mẹ́rin lára àwọn ìlànà Bíbélì tó ń ran àwọn èèyàn lọ́wọ́ kí wọ́n lè máa láyọ̀, kí ọkàn wọn sì túbọ̀ balẹ̀.

 

Àwọn Obìnrin inú Bíbélì​—Kí La Rí Kọ́ Lára Wọn?

Wo ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn obìnrin rere tí Bíbélì mẹ́nu kàn àtàwọn obìnrin búburú tó ṣe ohun tí kò dáa.

Kí Ni Ìpadàbọ̀ Kristi?

Ǹjẹ́ a máa lè fojú rí i tó bá dé?

Kí Nìdí Tí Jésù Fi Kú?

Báwo ni ikú rẹ̀ ṣe ṣe wá láǹfààní gan-an?

Kí Ló Túmọ̀ Sí Láti ‘Nífẹ̀ẹ́ Àwọn Ọ̀tá Wa’?

Kò rọrùn láti fi ọ̀rọ̀ tó ṣe kedere, tó sì nítumọ̀ tí Jésù sọ sílò.

Bá A Ṣe Lè Borí Ìkórìíra

Báwo lo ṣe lè borí ìkórìíra? Ka ìwé yìí kó o lè rí ìdáhùn ìbéèrè náà.

 

Ṣé Ìkórìíra Lè Dópin?

Ká tó lè borí ẹ̀tanú àti ìkórìíra, a gbọ́dọ̀ sapá gan-an láti mú un kúrò nínú ọkàn àti èrò wa. Wo ohun márùn-ún tá a lè ṣe láti gbógun ti ẹ̀tanú àti ìkórìíra.

Má Fìwà Jọ Àwọn Tó Mọ Tara Wọn Nìkan

Ọ̀pọ̀ èèyàn máa ń rò pé àwọn sàn ju àwọn mí ì lọ, wọ́n máa ń fẹ́ kí wọ́n fún wọn nípò pàtàkì láwùjọ, wọ́n sì máa ń rò pé ohun kan tọ́ sí àwọn. Wo àwọn ìlànà Bíbélì tó máa ràn ẹ́ lọ́wọ́ tí ò ní jẹ́ kó o nírú èrò yẹn.

Ìgbà wo ni òpin ayé máa dé?

Ṣé Bíbélì sọ ìgbà tó máa dé gan-an?

Ibo La Ti Lè Rí Òtítọ́?

Bíbélì sọ ìdáhùn tó jóòótọ́ nípa àwọn ìbéèrè pàtàkì tá a máa ń béèrè.