Ohun Tí Bíbélì Sọ
Kí ni Bíbélì fi kọ́ni gan-an? Mú ìbéèrè kan nínú àwọn ìbéèrè tó wà nísàlẹ̀ yìí.
Kí Ni Ẹranko Ẹhànnà Olórí Méje Inú Ìṣípayá Orí Kẹtàlá Dúró Fún?
Ẹranko ẹhànnà náà ní ọlá àṣẹ, ó ní agbára, ó sì ní ìtẹ́ kan. Kí tún ni àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì fi hàn wá?
Kí Ni Ẹranko Ẹhànnà Olórí Méje Inú Ìṣípayá Orí Kẹtàlá Dúró Fún?
Ẹranko ẹhànnà náà ní ọlá àṣẹ, ó ní agbára, ó sì ní ìtẹ́ kan. Kí tún ni àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì fi hàn wá?
Ọlọ́run
Bíbélì
Jésù
Ibi Tí Àwọn Ẹni Ẹ̀mí Ń Gbé
Ìyè àti Ikú
Ìyà
Ìgbàgbọ́ àti Ìjọsìn
Ìgbésí Ayé àti Ìwà Rere
Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Lọ́dọ̀ Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?—Èyí Tó Gùn
Bíbélì ń ran ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù èèyàn kárí ayé lọ́wọ́ láti rí ìdáhùn sí àwọn ìbéèrè pàtàkì nípa ìgbésí ayé. Ṣé ìwọ náà á fẹ́ jẹ́ ọ̀kan lára wọn?
Báwo La Ṣe Máa Ń Ṣe Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?
Níbi gbogbo kárí ayé làwọn èèyàn ti mọ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mọ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì tí wọ́n máa ń ṣe fáwọn èèyàn lọ́fẹ̀ẹ́. Wo bí wọ́n ṣe máa ń ṣe é.
Ṣé O Fẹ́ Ká Wá Ẹ Wá
O lè mọ̀ sí i nípa Bíbélì tàbí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.