Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Máa Ka Bíbélì Lójoojúmọ́

Máa Ka Bíbélì Lójoojúmọ́

Tó o bá ń ka Bíbélì, wàá gbádùn ẹ̀ gan-an! Díẹ̀ lára àwọn nǹkan tó lè ràn ẹ́ lọ́wọ́ nìyí. Yan àkòrí kan tó o fẹ́ràn, kó o sì ka àwọn ẹsẹ Bíbélì tó wà níbẹ̀.

Ìtàn Àwọn Èèyàn Tó Gbajúmọ̀

Ọ̀rọ̀ Ọgbọ́n Tó Wúlò fún Wa Lójoojúmọ́

Ohun Tó Lè Ràn Ẹ́ Lọ́wọ́ . . .

Ohun Tí Bíbélì Sọ Nípa . . .

ÀBÁ: Tó o bá fẹ́ mọ̀ sí i nípa àwọn ẹsẹ Bíbélì tó wà lókè yìí, ka àwọn orí Bíbélì náà látìbẹ̀rẹ̀ dópin. Bó o ṣe ń ka orí kọ̀ọ̀kan nínú Bíbélì, lo àtẹ náà “Sàmì sí Ibi Tó O Ka Bíbélì Dé” tó wà níparí ìwé yìí láti sàmì sí ibi tó o kà á dé. Gbìyànjú kó o máa ka Bíbélì lójoojúmọ́, ì báà tiẹ̀ jẹ́ díẹ̀ lo lè kà.