Privacy Settings

To provide you with the best possible experience, we use cookies and similar technologies. Some cookies are necessary to make our website work and cannot be refused. You can accept or decline the use of additional cookies, which we use only to improve your experience. None of this data will ever be sold or used for marketing. To learn more, read the Global Policy on Use of Cookies and Similar Technologies. You can customize your settings at any time by going to Privacy Settings.

Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Tá A Bá Tẹ̀ Lé Ìmọ̀ràn Tó Dáa Ó Máa Ṣe Wá Láǹfààní

Tá A Bá Tẹ̀ Lé Ìmọ̀ràn Tó Dáa Ó Máa Ṣe Wá Láǹfààní

Rèhóbóámù dojú kọ ipò tó gba pé kó ṣèpinnu (2Kr 10:1-4; w18.06 13 ¶3)

Rèhóbóámù ní káwọn míì gba òun nímọ̀ràn (2Kr 10:6-11; w01 9/1 28-29)

Rèhóbóámù kọ ìmọ̀ràn tó dáa tí wọ́n fún un, ìyẹn sì mú kí ìyà jẹ òun àti àwọn èèyàn náà (2Kr 10:12-16; it-2 768 ¶1)

Arábìnrin ọ̀dọ́ kan ń tẹ́tí sí arábìnrin àgbàlagbà kan bó ṣe ń sọ̀rọ̀ nílé oúnjẹ.

Àwọn àgbàlagbà tí òtítọ́ jinlẹ̀ nínú wọn tí wọ́n sì ní ìrírí máa ń mọ ibi tó ṣeé ṣe kí ọ̀rọ̀ kan já sí.​—Job 12:12.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Àwọn wo nínú ìjọ ló lè fún mi ní ìmọ̀ràn tó dáa?’