Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

August 4-10

ÒWE 25

August 4-10

Orin 154 àti Àdúrà | Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jésù ń bá àwọn èèyàn sọ̀rọ̀ ní sínágọ́gù tó wà ní Násárẹ́tì, ẹnu sì ń ya àwọn èèyàn bí wọ́n ṣe ń gbọ́ ọ̀rọ̀ tútù tó ń sọ

1. Àwọn Ìlànà Tó Kan Ọ̀rọ̀ Ẹnu Wa

(10 min.)

Mọ ìgbà tó yẹ kó o sọ̀rọ̀ (Owe 25:11; w15 12/15 19 ¶6-7)

Máa sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́, kó o sì máa sọ̀rọ̀ lọ́nà tó ń tuni lára (Owe 25:15; w15 12/15 21 ¶15-16; wo àwòrán)

Máa sọ̀rọ̀ tó ń gbéni ró (Owe 25:25; w95 4/1 17 ¶8)

2. Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì

(10 min.)

  • Owe 25:28—Kí ni òwe yìí túmọ̀ sí? (g19.3 6 ¶3)

  • Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí tí wàá fẹ́ sọ?

3. Bíbélì Kíkà

TẸRA MỌ́ IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

4. Bá A Ṣe Lè Bẹ̀rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Wa

(3 min.) ÌWÀÁSÙ ÀÌJẸ́-BÍ-ÀṢÀ. Bá ẹnì kan tí inú ẹ̀ ò dùn sọ̀rọ̀. (lmd ẹ̀kọ́ 3 kókó 3)

5. Pa Dà Lọ

(4 min.) ÌWÀÁSÙ ILÉ-DÉ-ILÉ. Ẹni náà sọ pé òun lẹ́sìn tòun, òun ò sì lè fi í lẹ̀. (lmd ẹ̀kọ́ 8 kókó 4)

6. Àsọyé

(5 min.) yp2 105-109—Àkòrí: Kí Ló Burú Nínú Kéèyàn Máa Sọ̀rọ̀ Ẹlòmíì Lẹ́yìn? (th ẹ̀kọ́ 13)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Orin 123

7. Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ

(15 min.)

8. Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ

Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min.) | Orin 150 àti Àdúrà