Nípa Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Ta Ni Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà wà kárí ayé. Jèhófà Ọlọ́run Olódùmarè tó dá ọ̀run àti ayé là ń jọ́sìn. (Sáàmù 83:18; Ìfihàn 4:11) Kristẹni ni wá, a sì gbà gbọ́ pé Jésù Kristi ni Ọmọ Ọlọ́run, òun sì ni Olùgbàlà wa. (Jòhánù 3:16; Ìṣe 4:10-12) Inú Bíbélì la ti rí gbogbo ohun tá a gbà gbọ́. (2 Tímótì 3:16) A rọ̀ ẹ́ pé kó o wo àwọn ohun tá a gbà gbọ́ lórí ìkànnì yìí, gbé Bíbélì ẹ dání, kó o sì máa wo àwọn ẹsẹ Bíbélì tí wọ́n tọ́ka sí nínú Bíbélì ẹ.
Wàá mọ púpọ̀ sí i nípa wa tó o bá wo fídíò Ta Ni Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
Iye
-
9,205,326—Iye àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà kárí ayé
-
119,652—Iye ìjọ
-
241—Iye orílẹ̀-èdè àti ìpínlẹ̀
-
7,603,182—Iye ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì tá à ń darí lọ́fẹ̀ẹ́ lóṣooṣù
-
20,635,015—Iye àwọn tó wá sí Ìrántí Ikú Kristi lọ́dún 2025
Frequently Asked Questions
Kí Ni Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Gbà Gbọ́?
Ní ṣókì, wo ohun mẹ́ẹ̀ẹ́dógún [15] tá a gbà gbọ́.
Kí Nìdí Táwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Kì Í Ṣe Àwọn Ayẹyẹ Kan?
Wo bá a ṣe dáhùn ìbéèrè pàtàkì mẹ́ta nípa àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó bá di ọ̀rọ̀ ayẹyẹ àtàwọn àjọ̀dún táwọn èèyàn máa ń ṣe.
Kí Nìdí Tí Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Kì Í Fí Ṣe Ayẹyẹ Ọjọ́ Ìbí?
Gbé àwọn kókó mẹ́rin nípa ayẹyẹ ọjọ́ ìbí tó jẹ́ ká mọ̀ pé Ọlọ́run kò nífẹ̀ẹ́ sí i yẹ̀ wò.
Ṣé Kristẹni Làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
Jọ̀wọ́ ṣàgbéyẹ̀wò bí a ṣe yàtọ̀ sí àwọn míì tí wọ́n ń pè ní Kristẹni.
Àwọn ìbéèrè míì táwọn èèyàn sábà máa ń béèrè
Wàá rí ìdáhùn sáwọn ìbéèrè tó o ní nípa wa.
Free Bible Course
Ìpàdé àti Àwọn Ìṣẹ̀lẹ̀ Pàtàkì
Contact Us
Ṣé O Fẹ́ Ká Wá Ẹ Wá
O lè mọ̀ sí i nípa Bíbélì tàbí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Lọ sí ìpàdé ìjọ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Wàá mọ ohun tá a máa ń ṣe láwọn ìpàdé wa, wàá sì mọ ibi tá a ti ń ṣèpàdé tó sún mọ́ ẹ.
Kàn sí Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Ìsọfúnni nípa bí ẹ ṣe lè kàn sí àwọn ẹ̀ka ọ́fíìsì wa jákèjádò ayé.
Ìbẹ̀wò sí Bẹ́tẹ́lì
O lè wá ibì kan tó sún mọ́ ẹ tó o lè ṣèbẹ̀wò sí.

